Jump to content

Aisha Falode

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Aisha Falode

Aisha Falode jẹ́ oniroyin fún èrè orí pàápàá ni Nàìjíríà. Òun ní olórí fún ẹgbẹ́ agbaboolu obìnrin fún orílè-èdè Nàìjíríà.[1][2] Ó wá láàrin àwọn òṣìṣẹ́ tí ó kọ́kọ́ bẹẹ rẹ̀ ní ilé iṣẹ́ telefisionu tí African Independent Television. Ó ti si ṣé pelu Nigerian Telecommunication Limited àti Graduate Telephone Operators Scheme.[3][4][5] Ó jẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ lórí rádíiò, ó sì má sọ̀rọ̀ nípa eré orí pàápàá.[6] Ní oṣù kìíní ọdún 2017, wọn fi jẹ olórí ẹgbẹ́ agbaboolu obìnrin fún orílè-èdè Nàìjíríà.[7]

Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. "NWFL board mourns death of Nasarawa Amazons chairman". Premium Times Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-03-04. Retrieved 2019-04-07. 
  2. Newspapers, BluePrint (2019-03-31). "Lagos agog for AITEO/NFF event, FIFA Scribe set to pick award". Blueprint (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2019-04-07. 
  3. BellaNaija.com (2014-05-04). "Aisha Falode seeks Justice for her 19 Year Son Toba who died in Dubai". BellaNaija (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2019-04-07. 
  4. "I love Jean trousers and T-shirts - Falode". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2012-03-15. Retrieved 2019-04-07. 
  5. "Asia is fast becoming dominant in football - Aisha Falode". The Nation Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2017-03-17. Retrieved 2019-04-07. 
  6. "Archived copy". Archived from the original on 2014-02-15. Retrieved 2014-08-13.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  7. "Aisha Falode inaugurated board chair of Nigeria Women Football League". Premium Times. Retrieved 2017-10-05.